Ìwé Kíróníkà Kìn-ín-ní 1:1-54 BYB2014 - Bible AI

1ⓐ Ádámù, Ṣétì, Énọ́sì,

2Kénánì, Máháláléélì, Jérédì,

3Hénókì, Mètúsẹ́là, Lámékì, Nóà.

4Àwọn ọmọ Nóà, Ṣémù, Ámù àti Jáfétì.

5Àwọn ọmọ Jáfétì:

5Gómérì, Mágógù, Mádà; Jáfánì, Túbálì, Méṣékì, Tírásì

6Àwọn ọmọ Gómérì:

6Áṣíkénásì, Bífátì, Tógárímà.

7Àwọn ọmọ Jáfánì:

7Èlíṣà, Tárísísì, Kítímù, àti Dódánímù.

8Àwọn ọmọ Ámù:

8Kúṣì, Ṣébà, Mísíráímù, Pútì, àti Kénánì.

9Àwọn ọmọ Kúṣì: Àwọn ọmọ Rámà: Ṣébà àti Dédánì.

9Ṣébà Háfílà, Ṣébítà, Rámà, àti Ṣábítékà,

10Kúṣì ni baba Nímíródù:

10Ẹni tí ó dàgbà tí ó sì jẹ́ jagunjagun alágbára lórí ilẹ̀ ayé.

11Mísíráímù ni baba

11Lúdímù, Ánámímù, Léhábímù, Náfítúhímù,

12Pátírísímù, Kásiliúhímù, (Láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Fílístínì ti wá) àti Káfitórímù.

12

13Kénánì ni baba

13Ṣídónì àkọ́bí Rẹ̀, àti ti àwọn ará Hítì,

14Àwọn ará Jébúsì, àwọn ará Ámórì, àwọn ará Gírígásì

15Àwọn Hífì, àwọn ará Áríkì, àwọn ará Hamati-Ṣínì,

16Àwọn ará Árífádù, àwọn ará, Ṣémárì, àwọn ará Hámátì.

16

17Àwọn ọmọ Ṣémù: Àwọn ará Árámù: Usì Húlì, Gétérì, àti Méṣékì.

17Élámù. Ásúrì, Árífákásádì, Lúdì àti Árámù.

18Árífákásádì sì jẹ́ Baba Ṣélà,

18àti Ṣélà sì jẹ́ Baba Ébérì.

19A bí àwọn ọmọ méjì fún Ébérì:

19Orúkọ ọ̀kan ni Pélégì, nítorí ní àkókò tirẹ̀ a pín ayé; orúkọ ẹ̀gbọ́n Rẹ̀ ọkùnrin a sì máa jẹ́ Jókítanì.

20Jókítanì sì jẹ́ Baba fún

20Hímódádì, Ṣéléfì, Hásárímáfétì, Jérà.

21Hádórámì, Úsálì, àti Díkílà

22Ébálì, Ábímáélì, Ṣébà.

23Ófírì, Háfílà, àti Jóbábù. Gbogbo àwọn wọ̀nyí sì jẹ́ àwọn ọmọ Jókítanì.

23

24Ṣémù, Árífákásádì, Sẹ́bà,

24

25Ébérì, Pélégì. Réù,

25

26Ṣérúgì, Náhórì, Térà:

26

27Àti Ábúrámù (tí ń ṣe Ábúráhámù).

27

28Àwọn ọmọ Ábúráhámù:

28Ísáákì àti Íṣímáẹ́lì.

29Èyí ni àwọn ọmọ náà:

29Nébáíótì àkọ́bí Íṣímáẹ́lì: Kédárì, Ádíbélì, Míbísámù,

30Míṣímà, Dúmà, Másà, Hádádì, Témà,

31Jétúrì, Náfísì, àti Kédámù. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Íṣímáẹ́lì

31

32Àwọn ọmọ Kétúrà, obìnrin Ábúráhámù: Àwọn ọmọ Jókísánì: Ṣébà àti Dédánì.

32Símíránì, Jókíṣánì Médánì, Mídíánì Iṣíbákì àti Ṣúà.

33Ọmọ Mídíánì: Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Kétúrà.

33Éfà. Hénókì, Éférì, Ábídà àti Élídà.

34Ábúráhámù sì jẹ́ baba Ísáákì: Ísọ̀ àti Ísírẹ́lì.

34Àwọn ọmọ Ísáákì:

35Àwọn ọmọ Ísọ̀:

35Élífásì, Réuélì, Jéúsì, Jálámù, àti Kórà.

36Àwọn ọmọ Élífásì: làti Tímánà: Ámálékì.

36Témánì, Ómárì, Ṣéfì, Gátamù àti Kénásì;

37Àwọn ọmọ Réúélì:

37Náhátì, Ṣérà, Ṣámà àti Mísà.

38Àwọn ọmọ Ṣéírì:

38Lótanì, Ṣóbálì, Ṣíbéónì, Ánà, Díṣónì, Ésárì àti Dísánì.

39Àwọn ọmọ Lótanì:

39Hórì àti Hómámù. Tímínà sì jẹ́ arábìnrin Lótanì.

40Àwọn ọmọ Ṣóbálì: Àwọn ọmọ Ṣíbéónì: Áíyà àti Ánà.

40Álíánì, Mánánátì, Ébálì, Ṣéfì àti Ónámù.

41Àwọn ọmọ Ánà: Àwọn ọmọ Díṣónì: Hémídánì, Éṣébánì, Ítíránì, àti Kéránì.

41Díṣónì.

42Àwọn ọmọ Èsérì: Àwọn ọmọ Díṣánì: Húsì àti Áránì.

42Bílíhánì, Ṣáfánì àti Jákánì.

43Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Édómù, kí ó tó di wí pé àwọn ọba ará Ísírẹ́lì kán jẹ:

43Bélà ọmọ Béórì, ẹni tí orúkọ ìlú Rẹ̀ a máa jẹ́ Díníhábà.

44Nígbà tí Bélà kú, Jóbábù ọmọ Ṣérà láti Bósírà jẹ ọba dípò Rẹ̀.

44

45Nígbà tí Jóbábù sì kú, Húṣámù láti ilẹ̀ àwọn ará Témánì sì jẹ ọba ní ipò Rẹ̀.

45

46Nígbà tí Húṣámù sì kú, Hádádì ọmọ Bédádì, ẹni tí ó kọlu Mídíánì ní agbégbé Móábù, ó sì jẹ ọba ní ipò Rẹ̀. Orúkọ ìlú Rẹ̀ sì ni Áfítì.

46

47Nígbà tí Hádádì sì kú, Ṣámílà láti Másírékà, ó sì jọba ní ipò Rẹ̀

47

48Nígbà tí Ṣámílà sì kú, Ṣáúlì láti Réhóbótì lórí odò sì jẹ ọba ní ipò Rẹ̀

48

49Nígbà tí Ṣáúlì sì kú, Báli-hánánì, ọmọ Ákíbórì sì jẹ ọba ní ipò Rẹ̀.

49

50Nígbà tí Báli-hánánì sì kú, Hádádì sì di ọba nípò Rẹ̀. Orúkọ ìlú Rẹ̀ sì ni Páì; àti orúkọ ìyàwó sì ni Méhélábélì ọmọbìnrin Métírédì, ọmọbìnrin Mésíhábù.

51Hádádì sì kú pẹ̀lú. Tímínà, Álífà, Jététì

51Àwọn olórí Édómù ni:

52Óhólíbámà, Élà, Pínónì.

53Kénásì, Témánì, Mísárì,

54Mágádíẹ́lì àti Ìrámù. Àwọn wọ̀nyí ni Olórí Édómù.

article>