1Àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé OLÚWA yóò dàbí òkè Síónì, tí a kò lè sí ní ìdí, bí kò ṣe pé ó dúró láéláé
2Bí òkè ńlá ti yí Jérúsálẹ́mù ká, bẹ́ẹ̀ ní OLÚWA yí ènìyàn ká láti ìsinsìnyí lọ àti títí láéláé.
3Nítorí tí ọ̀pá àwọn ènìyàn búburú kì yóò bà lé ìpín àwọn olódodo; kí àwọn olódodo kí o máa ba fi ọwọ́ wọn lé ẹ̀ṣẹ̀.