Ìwé Sáàmù 128:1-6 BYB2014 - Bible AI

1Ìbùkún ni fún gbogbo ẹni tí ó bẹ̀rù OLÚWA: tí ó sì ń rìn ní ọ̀nà Rẹ̀

2Nítorí tí ìwọ yóò jẹ isẹ́ ọwọ́ Rẹ ìbùkún ni fún ọ; yóò sì dára fún ọ

3Obìnrin Rẹ yóò dà bí àjàrà rere eléso púpọ̀ ní àárin ilé Rẹ; àwọn ọmọ Rẹ yóò dà bí igi olífì tí ó yí tábìlì Rẹ ká.

4Kíyèsíi pé, bẹ́ẹ̀ ni a o bù síi fún ọkùnrin náà, tí o bẹ̀rù OLÚWA.

4

5Kí OLÚWA kí o bù síi fún ọ láti Síónì wá, kí ìwọ kí ó sì máa rí ire Jérúsálẹ́mù ní ọjọ́ ayé Rẹ gbogbo.

6Bẹ́ẹ̀ ni kí ìwọ kí o sì máa rí àti ọmọ dé ọmọ Rẹ; àti àlàáfíà lára Ísírẹ́lì.

Copyright © 2014 by Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide
v>